Nigerian Law School

Àdàkọ:Infobox law school

Nigerian Law School jẹ́ ilé-ẹ̀kọ́ tí ìjọba gbé kalẹ̀ ní ọdún 1962 fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ́ìmọ̀ Òfin yálà ní ́abẹ́lé ni tàbí fún àwọn akẹ́kọ̀ọ́ òkè-òkun ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1] Àwọn tí wọ́n nífẹ̀ẹ́ sí iṣẹ́ ìmọ̀ òfin ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ṣáájú ọdún 1962 ti ìjọba gbé ilé-ẹ̀kọ́ yi kalẹ̀ ni wọ́n ma ń lọ kọ́ èkọ́ ìmọ̀ òfin ní orílẹ-èdè England tí wọn sì ma ń ṣiṣẹ́ gẹ́gẹ́ bi amòfin ní ìlú náà .[2]

  1. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named self
  2. Leesi Ebenezer Mitee (29 March 2008). "Introduction to Nigerian Legal Education". Nigerian Law Resources. Archived from the original on 14 July 2011. Retrieved 21 November 2009.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)

From Wikipedia, the free encyclopedia · View on Wikipedia

Developed by Tubidy